Sáàmù 53:2-5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

2. Ọlọ́run bojú wo ilẹ̀ láti ọ̀runsórí àwọn ọmọ ènìyànláti wò bóyá ẹnìkan wà tí ó ní òye,tí ó sì ń wá Ọlọ́run.

3. Gbogbo ènìyàn tí ó ti yí padà,wọ́n ti parapọ̀ di ìbàjẹ́;kò sí ẹnìkan tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.

4. Ṣé àwọn oníṣẹ́ búburú kò ní ìmọ̀?Àwọn ẹni tí ń jẹ ènìyàn mi, bí ẹni jẹuntí wọn kò sì pe Ọlọ́run?

5. Níbẹ̀ ni ìwọ gbé wà ní ìbẹ̀rù ńláníbì tí ẹ̀rù kò gbé sínítorí Ọlọ́rún tí fọ́n egungun àwọn tí ó dótì ọ́ ká;ìwọ tí dójú tì wọ́n, nítorí Ọlọ́run ti kẹ́gàn wọn.

Sáàmù 53