Sáàmù 88:15-18 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

15. Láti ìgbà èwe mi, ìṣẹ́ ń ṣẹ́ mi,èmi múra àti kú;nígbà ti ẹ̀ru Rẹ ba ń bà mí,èmi di gbére-gbère

16. Ìbínú Rẹ ti kọjá lára mi;ìbẹ̀rù Rẹ ti ge mi kúrò

17. Ní gbogbo ọjọ́ ní wọn yí mi ká bí ìkún omi;wọ́n mù mí pátápátá.

18. Ìwọ ti mú ọ̀rẹ́ àti olùfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ mi;òkùnkùn sì jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi.

Sáàmù 88