Sáàmù 56:1 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, nítorí àwọn ènìyàn ń fi ìgbọ́nára lépa mi;ní gbogbo ọjọ́ ni wọn ń kọjú ìjàsí mi, wọn ń ni mi lára.

Sáàmù 56

Sáàmù 56:1-4