21. Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ti ṣe, mo sì dákẹ́;ìwọ rò pé mo jẹ́ irú kan náà bí ìrẹ,ṣùgbọ́n èmi yóò bá ọ wíèmi yóò sì fi ẹ̀sùn kàn ọ́ ní ojú ara Rẹ.
22. “Ǹjẹ́ ìwọ ro èyí wò, ẹ̀yin tí ó gbàgbé Ọlọ́runBí bẹ́ ẹ̀ kọ́ èmi yóò fa yin ya pẹ́rẹ́pẹ̀rẹ́láì sí ẹni tí yóò gbà yin sílẹ̀
23. Ẹni tí ó ba ní ẹbọ ọrẹ ọpẹ́ bu ọláfún mi; kí ó sì tún ọ̀nà Rẹ̀ ṣekí èmi kí ó le fi ìgbàlà Ọlọ́run hàn án.”