Jòhánù 14:29-31 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

29. Èmi sì ti sọ fún yín nísinsìn yìí kí ó tó ṣẹ, pé nígbà tí ó bá ṣẹ, kí ẹ lè gbàgbọ́.

30. Èmi kì ó bá yín sọ̀rọ̀ púpọ: nítorí aláde ayé yí wá, kò sì ní nǹkankan lọ́dọ̀ mi.

31. Ṣùgbọ́n nítorí kí ayé lè mọ̀ pé èmi fẹ́ràn Baba; gẹ́gẹ́ bí Baba sì ti fi àṣẹ fún mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi ń ṣe.“Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a lọ kúrò níhínyìí.

Jòhánù 14