Jeremáyà 51:28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Pèsè àwọn orílẹ̀ èdè láti bá jagun,àwọn Ọba Médíà, Gómìnà àti gbogboọmọ ìgbìmọ̀ wọn àti gbogbo orílẹ̀ èdè tí wọ́n jọba lé lórí.

Jeremáyà 51

Jeremáyà 51:26-31