Ìṣe Àwọn Àpósítélì 20:30 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Láàrin ẹ̀yin tìkárayín ni àwọn ènìyàn yóò sì dìde, tí wọn yóò máa sọ̀rọ̀-òdì, láti fa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sẹ́yìn wọn.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 20

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 20:23-31