Ìṣe Àwọn Àpósítélì 2:24 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run jí díde kúrò nínú òkú, gbà á kúrò nínú ìrora ikú: nítorí tí kò ṣe é ṣe fún ikú láti dì í mú.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 2

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 2:23-27