Ìṣe Àwọn Àpósítélì 1:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà, nígbà tí wọ́n sì péjọ pọ̀, wọn bi í léèrè pé, “Olúwa, láti ìgbà yí lọ ìwọ yóò ha mú ìjọba padà fún Ísírẹ́lì bí?”

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 1

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 1:1-13