Ámósì 9:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Òun ni ẹni tí ó kọ́ itẹ́ rẹ̀ nínú àwọn ọ̀runti ó sì fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ ní ilé ayéẸni ti ó pe àwọn omi òkunti ó sì tú wọn jáde si orí ilé ayé Olúwa ni orúkọ rẹ̀.

Ámósì 9

Ámósì 9:1-9