2 Sámúẹ́lì 24:2 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ọba sì wí fún Jóábù Olórí ogun, tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Lọ ní ìsinsìnyìí sí gbogbo ẹ̀yà Ísírẹ́lì láti Dánì títí dé Bíásébà, kí ẹ sì ka iye àwọn ènìyàn, kí èmi lè mọ iye àwọn ènìyàn náà!”

2 Sámúẹ́lì 24

2 Sámúẹ́lì 24:1-9