Sáàmù 46:5-11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

5. Ọlọ́run wà pẹ̀lú Rẹ̀, kò ní yẹ̀:Ọlọ́run yóò ràn an lọ́wọ́ ní kùtùkùtù ọ̀wúrọ̀

6. Àwọn orílẹ̀ èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba subúó gbé ohun Rẹ̀ sókè, ayé yọ̀.

7. Ọlọ́run awọn ọmọ ogún wà pẹ̀lú waỌlọ́run Jákọ́bù ni ààbò wa

8. Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwairú ahoro tí ó ṣe ní ayé

9. O mú ọ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayéó ṣẹ́ ọrun, ó sì gé ọ̀kọ̀ sí méjìó fi kẹ̀kẹ́ ogun jóná

10. Ẹ dúró jẹ́ẹ kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́runA ó gbé mi ga nínú àwọn orílẹ̀ èdèA o gbé mi ga ní ayé.

11. Ọlọ́run alágbára wà pẹ̀lú waỌlọ́run Jákọ́bù sì ni ààbò wa.

Sáàmù 46