Sáàmù 41:1-4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ìbùkùn ni fún ẹni tí ó ń rò ti aláìní: Olúwa yóò gbà á ni ìgbà ìpọ́njú.

2. Olúwa yóò dààbò bòó yóò sí pa ọkàn Rẹ̀ mọ́:yóò bùkún fún-un ni orí ilẹ̀kò sì ní fi sílẹ̀ fún ìfẹ́ àwọn ọ̀tá Rẹ̀.

3. Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn Rẹ̀yóò sì mú-un padà bọ̀ sípò kúrò nínú àìsàn Rẹ̀.

4. Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mí;wò mí sàn, nítorí pé mo ti ṣẹ̀ sí ọ”.

Sáàmù 41