Sáàmù 31:20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ní abẹ́ ibòji iwájú Rẹ ni ìwọ pa wọ́n mọ́ síkúrò nínú ìdìmọ̀lù àwọn ènìyàn;ní ibùgbé Rẹ o mú wọn kúrò nínú ewukúrò nínú ìjà ahọ́n.

Sáàmù 31

Sáàmù 31:10-24