Sáàmù 27:3 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Bí ọmọ ogun tilẹ̀ yí mi ká tí wọ́n sì dìde sí mi,ọkàn mi kì yóò bẹ̀rù;bí ogun tilẹ̀ dìde sí mi,nínú èyí ni ọkàn mi yóò le.

Sáàmù 27

Sáàmù 27:1-5