Sáàmù 10:9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

O lúgọ ní bùba nínú pàǹtí;ó lúgọ ní bùba làti mú àwọn aláìní ìrànwọ́;ó mú àwọn aláìlólùrànlọ́wọ́, ó sì wọ́ wọn lọ sínú àwọ̀n Rẹ̀.

Sáàmù 10

Sáàmù 10:1-18