Nehemáyà 6:2 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣáńbálátì àti Géṣémù rán iṣẹ́ yìí sí mi pé: “Wá jẹ́ kí a jọ pàdé pọ̀ nínú ọ̀kan lára àwọn ìletò ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Ónò.”Ṣùgbọ́n wọ́n ń gbérò láti ṣe mí ní ibi;

Nehemáyà 6

Nehemáyà 6:1-7