Lúùkù 1:76 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Àti ìwọ, ọmọ mi, wòlíì Ọ̀gá-ògo jùlọ ni a ó máa pè ọ́:Nítorí ìwọ ni yóò ṣáájú Olúwa láti tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe;

Lúùkù 1

Lúùkù 1:71-79