27. Ẹni tí èmi ó rí fún ara mi, tí ojúmi ó sì wo, kì sì íṣe tiẹlòmìíràn; ọkàn mi sì dákú ní inú mi.
28. “Bí ẹ̀yin bá wí pé, ‘àwa ó ti lépa rẹ̀ tó!Àti pé, gbogbo ọ̀rọ̀ náà ni a ṣáà rí ní ọwọ́ rẹ̀,’
29. Kí ẹ̀yin kí ó bẹ̀rù; nítorí ìbínú níímú ìjìyà wá nípa ìdàKí ẹ̀yin kí ó lè mọ̀ pé ìdájọ́ kan ń bẹ.”