Jóẹ́lì 2:1 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ẹ fun ìpè ní Ṣíónì,ẹ sì fún ìpè ìdágàrì ní òkè mímọ́ mi.Jẹ́ kí àwọn ará ilẹ̀ náà wárìrì,nítorí tí ọjọ́ Olúwa ń bọ̀ wá,nítorí ó kù sí dẹ̀dẹ̀.

Jóẹ́lì 2

Jóẹ́lì 2:1-7