Jeremáyà 27:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kí o sì pàṣẹ fún wọn láti wí fún àwọn olúwa wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì wí: “Sọ èyí fún àwọn olúwa rẹ:

Jeremáyà 27

Jeremáyà 27:3-8