Jẹ́nẹ́sísì 3:23 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà, Olúwa Ọlọ́run lé e kúrò nínú ọgbà Édẹ́nì láti lọ máa ro ilẹ̀ nínú èyí tí a ti mú un jáde wá.

Jẹ́nẹ́sísì 3

Jẹ́nẹ́sísì 3:21-24