Jẹ́nẹ́sísì 14:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àfonífojì Ṣídímù sì kún fún kòtò ọ̀dà-ilẹ̀, nígbà tí ọba Ṣódómù àti ọba Gòmórà sì ṣá, díẹ̀ nínú àwọn ọkùnrin ogun náà subú sínú àwọn kòtò náà, àwọn tókù sì sálọ sì orí òkè.

Jẹ́nẹ́sísì 14

Jẹ́nẹ́sísì 14:5-19