Ísíkẹ́lì 26:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ìlú tí ó tẹ̀dó sí, ní àárin gbùngbùn ilẹ̀ rẹ̀ ni a ó fi idà sọ ọ́ di ahoro. Nígbà náà ní wọn yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa.

Ísíkẹ́lì 26

Ísíkẹ́lì 26:2-7