Ìfihàn 15:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ta ni kì yóò bẹ̀rù, Olúwa,tí kì yóò sì fi ògo fún orúkọ rẹ̀?Nítorí ìwọ níkanṣoṣo ni mímọ́.Gbogbo àwọn orílẹ èdè mi yóò sì wá,ti yóò sì foribalẹ̀ níwájú rẹ,nítorí a ti fi ìdájọ́ rẹ hàn.”

Ìfihàn 15

Ìfihàn 15:1-8