Ìfihàn 14:10 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Òun pẹ̀lú yóò mú nínú ọtí-wáìnì ìbínú Ọlọ́run, tí a dà láìní àbùlà sínú ago ìrúnnú rẹ̀; a ó sì fi iná sufúrù dá a lóró níwájú àwọn ańgẹ́lì mímọ́, àti níwájú Ọ̀dọ́-Àgùntàn:

Ìfihàn 14

Ìfihàn 14:4-13