Ìṣe Àwọn Àpósítélì 8:22 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà ronúpìwàdà ìwà búrurú rẹ yìí, kí ó sì gbàdúrà sọ́dọ̀ Ọlọ́run bóyá yóò dári ète ọkàn rẹ jì ọ́.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 8

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 8:17-27