Ìṣe Àwọn Àpósítélì 24:19 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n àwọn Júù kan láti ẹkùn Éṣíà wà níbẹ̀, àwọn tí ì bá wà níhìn-ín yìí níwájú rẹ, kí wọn já mi nírọ́, bí wọ́n bá ní ohunkohun sí mi.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 24

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 24:18-24