Ìṣe Àwọn Àpósítélì 22:2 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí wọ́n sì gbọ́ pé ó ń bá wọn sọ̀rọ̀ ni èdè Árámáíkì, wọ́n túbọ̀ dákẹ́ jẹ́ẹ́.Nígbà náà ni ó wí pé:

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 22

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 22:1-5