Ìṣe Àwọn Àpósítélì 22:11 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àwọn tí ó sì wà pẹ̀lú mi fà mí lọ́wọ́ wọ Dámásíkù lọ nítorí tí èmi kò lè ríran nítorí ìtànṣán ìmọ́lẹ̀ náà ti fọ́ mi ní ojú.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 22

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 22:8-20