Ìṣe Àwọn Àpósítélì 2:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nítorí náà inú mi dùn, ahọ́n mi sì yọ̀:pẹ̀lúpẹ̀lú ara mi yóò sì sinmi ní ìrètí.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 2

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 2:23-34