Ìṣe Àwọn Àpósítélì 18:5 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí Sílà àti Tímótíù sì tí Makedóníà wá, ọ̀rọ̀ náà ká Pọ́ọ̀lù lára, ó ń fi hàn fún àwọn Júù pé, Jésù ni Kírísítì náà.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 18

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 18:1-7