Ìṣe Àwọn Àpósítélì 18:12 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí Gálíónì sì jẹ báalẹ̀ Ákáyà, àwọn Júù fi ìfìmọ̀ṣọ̀kan dide sí Pọ́ọ̀lù wọn sì mú un wá síwájú ìtẹ́ ìdájọ́.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 18

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 18:5-14