Ìṣe Àwọn Àpósítélì 16:35 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n nígbà tí ilẹ̀ mọ́, àwọn onídájọ́ rán àwọn ọlọ́pàá pé, “Tú àwọn ènìyàn náà ṣílẹ̀.”

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 16

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 16:34-36