Ìṣe Àwọn Àpósítélì 13:6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nígbà tí wọ́n sì la gbogbo erékùṣù já dé Páfọ̀, wọ́n rí ọkùnrin kan, oṣó, wòlíì èké, Júù, orúkọ ẹni ti ó ń jẹ́ Baa-Jésù.

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 13

Ìṣe Àwọn Àpósítélì 13:4-13