Ẹkún Jeremáyà 2:19 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Dìde, kígbe sókè ní àsálẹ́,bí ìṣọ́ òru ti bẹ̀rẹ̀tú ọkàn rẹ̀ jáde bí ominíwájú Olúwa.Gbé ọwọ́ yín sókè sí inítorí ẹ̀mí àwọn èwe rẹ̀tí ó ń kú lọ nítorí ebiní gbogbo oríta òpópó.

Ẹkún Jeremáyà 2

Ẹkún Jeremáyà 2:16-22