Ékísódù 6:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Árónì àti Mósè yìí kan náà ni Olúwa sọ fún pé, “Ẹ kó àwọn ará Ísírẹ́lì jáde kúrò ni ilẹ̀ Éjíbítì ní ìsọ̀rí ìsọ̀rí.”

Ékísódù 6

Ékísódù 6:25-27