Ékísódù 40:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Gbé tábìlì náà wọ ilé, kí o sì tò àwọn ohun tí ó jẹ́ tirẹ̀ lé e lórí. Nígbà náà gbé ọ̀pá fìtílà wọlé, kí o sì to àwọn fìtílà rẹ̀.

Ékísódù 40

Ékísódù 40:1-6