Deutarónómì 23:20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

O lè ka èlé sí àlejò lọ́rùn, ṣùgbọ́n kì í ṣe arákùnrin ọmọ Ísírẹ́lì, nítorí kí Olúwa Ọlọ́run rẹ lè bùkún ọ nínú ohun gbogbo tí o bá dáwọ́ lé ní ilẹ̀ tí ò ń wọ̀ lọ láti ní.

Deutarónómì 23

Deutarónómì 23:17-24