Deutarónómì 20:16 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ṣùgbọ́n, nínú àwọn ìlú ti àwọn orílẹ̀ èdè tí Olúwa Ọlọ́run rẹ ń fún ọ gẹ́gẹ́ bí ogún, má ṣe dá ohun ẹlẹ́mìí kankan sí.

Deutarónómì 20

Deutarónómì 20:7-20