2 Ọba 24:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Àti pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ tí a ta sílẹ̀ nítorí ó ti kún Jérúsálẹ́mù pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ tí Olúwa kò sì fẹ́ láti dáríjìn.

2 Ọba 24

2 Ọba 24:1-8