2 Ọba 21:18 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Mánásè sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ wọ́n sì sin ín nínú ọgbà ààfin rẹ̀, ọgbà Úṣà Ámónì ọmọ rẹ̀ sì jọba ní ipò rẹ̀.

2 Ọba 21

2 Ọba 21:11-19