1 Ọba 14:20 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Jéróbóámù sì jọba fún ọdún méjìlélógún, ó sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀. Nádábù ọmọ rẹ̀ sì jọba ní ipò rẹ̀.

1 Ọba 14

1 Ọba 14:16-25