1 Kíróníkà 6:11-19 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

11. Áṣáríyà baba ÁmáríyàÁmáríyà baba Áhítúbì

12. Áhítúbì baba Ṣádókù.Ṣádókù baba Ṣálúmù,

13. Ṣálúmù baba Hílíkíyà,Hílíkíyà baba Áṣáríyà,

14. Áṣáríyà baba Ṣéráíà,pẹ̀lú Ṣéráíà baba Jéhósádákì

15. A kó Jéhósádákì lẹ́rú nígbà tí Olúwa lé Júdà àti Jérúsálẹ́mù kúrò ní ìlú nípaṣẹ̀ Nebukadinésárì.

16. Àwọn ọmọ Léfì:Gérísónì, kóhátì àti Mérárì.

17. Wọ̀nyí ni àwọn orúkọ àwọn ọmọ Géríṣónì:Líbínì àti Ṣíméhì.

18. Àwọn ọmọ Kéhátì:Ámírámù, Íṣárì, Hébírónì àti Húsíélì.

19. Àwọn ọmọ Mérárì:Máhílì àti Múṣì.Wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ará Léfì tí a kọ ní ṣíṣẹ̀ ń tẹ̀lé gẹ́gẹ́ bí baba wọn:

1 Kíróníkà 6