1 Kíróníkà 2:39-55 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

39. Ásáríyà sì ni baba Hélésì,Hélésì ni baba Éléáṣáì,

40. Éléáṣáì ni baba Ṣísámálì,Ṣísámálì ni baba Ṣálúmù,

41. Ṣálúmù sì ni baba Élísámà.

42. Àwọn ọmọ Kálébù arákùnrin Jérámélì:Méṣà àkọ́bí Rẹ̀, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Ṣífì àti àwọn ọmọ Rẹ̀ Méréṣà, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Hébúrónì.

43. Àwọn ọmọ Hébúrónì:Kórà, Tápúà, Rékémù, àti Ṣémà.

44. Ṣémà ni baba Ráhámú Ráhámù sì jẹ́ baba fún Jóríkéámù. Rékémù sì ni baba Ṣémáì.

45. Àwọn ọmọ Ṣémáì ni Máónì, Máónì sì ni baba Bétí-Ṣúri.

46. Éfà Obìnrin Kélẹ́bù sì ni ìyá Hárà nì, Mósà àti Gásésì, Háránì sì ni baba Gásésì.

47. Àwọn ọmọ Jádáì:Régémù, Jótamù, Gésánì, Pétélì, Éfà àti Ṣáfù.

48. Mákà obìnrin Kélẹ́bù sì ni ìyá Ṣébérì àti Tíránà.

49. Ó sì bí Ṣáfà baba Mákíbénà, Ṣéfà baba Mákíbénà àti baba Gíbéà: ọmọbìnrin Kélẹ́bù sì ni Ákíṣà.

50. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kélẹ́bù.Àwọn ọmọ Húrì, àkọ́bí Éfúrátà:Ṣóbálì baba Kiriati-Jéárímù.

51. Ṣálímà baba Bétíléhẹ́mù àti Háréfù baba Bẹti-Gádérì.

52. Àwọn ọmọ Ṣóbálì baba Kíríátì-Jéárímù ni:Háróè, ìdajì àwọn ará Mánáhítì.

53. Àti ìdílé Kíríátì-Jéárímù: àti àwọn ara Ítírì, àti àwọn ará Pútì, àti àwọn ará Ṣúmátì àti àwọn ará Mísíhí-ráì: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sórátì àti àwọn ará Ésítaólì ti wá.

54. Àwọn ọmọ Ṣálímà:Bẹ́tílẹ́hẹ́mù, àti àwọn ará Nétófátì, Atírótì Bẹti-Jóábù, ìdajì àwọn ará Mánátì, àti Ṣórì,

55. Àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jábésì: àti àwọn ọmọ Tírátì àti àwọn ará Ṣíméátì àti àwọn ará Ṣúkátì. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Kénì, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hámátì, baba ilé Kélẹ́bù.

1 Kíróníkà 2