1 Kíróníkà 1:33-52 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

33. Ọmọ Mídíánì:Éfà. Hénókì, Éférì, Ábídà àti Élídà.Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Kétúrà.

34. Ábúráhámù sì jẹ́ baba Ísáákì:Àwọn ọmọ Ísáákì:Ísọ̀ àti Ísírẹ́lì.

35. Àwọn ọmọ Ísọ̀:Élífásì, Réuélì, Jéúsì, Jálámù, àti Kórà.

36. Àwọn ọmọ Élífásì:Témánì, Ómárì, Ṣéfì, Gátamù àti Kénásì;làti Tímánà: Ámálékì.

37. Àwọn ọmọ Réúélì:Náhátì, Ṣérà, Ṣámà àti Mísà.

38. Àwọn ọmọ Ṣéírì:Lótanì, Ṣóbálì, Ṣíbéónì, Ánà, Díṣónì, Ésárì àti Dísánì.

39. Àwọn ọmọ Lótanì:Hórì àti Hómámù. Tímínà sì jẹ́ arábìnrin Lótanì.

40. Àwọn ọmọ Ṣóbálì:Álíánì, Mánánátì, Ébálì, Ṣéfì àti Ónámù.Àwọn ọmọ Ṣíbéónì:Áíyà àti Ánà.

41. Àwọn ọmọ Ánà:Díṣónì.Àwọn ọmọ Díṣónì:Hémídánì, Éṣébánì, Ítíránì, àti Kéránì.

42. Àwọn ọmọ Èsérì:Bílíhánì, Ṣáfánì àti Jákánì.Àwọn ọmọ Díṣánì:Húsì àti Áránì.

43. Àwọn wọ̀nyí ni ọba tí ó jẹ ní Édómù, kí ó tó di wí pé àwọn ọba ará Ísírẹ́lì kán jẹ:Bélà ọmọ Béórì, ẹni tí orúkọ ìlú Rẹ̀ a máa jẹ́ Díníhábà.

44. Nígbà tí Bélà kú, Jóbábù ọmọ Ṣérà láti Bósírà jẹ ọba dípò Rẹ̀.

45. Nígbà tí Jóbábù sì kú, Húṣámù láti ilẹ̀ àwọn ará Témánì sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀.

46. Nígbà tí Húṣámù sì kú, Hádádì ọmọ Bédádì, ẹni tí ó kọlu Mídíánì ní agbégbé Móábù, ó sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀. Orúkọ ìlú Rẹ̀ sì ni Áfítì.

47. Nígbà tí Hádádì sì kú, Ṣámílà láti Másírékà, ó sì jọba ní ipò Rẹ̀

48. Nígbà tí Ṣámílà sì kú, Ṣáúlì láti Réhóbótì lórí odò sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀

49. Nígbà tí Ṣáúlì sì kú, Báli-hánánì, ọmọ Ákíbórì sì jẹ ọba ní ipò Rẹ̀.

50. Nígbà tí Báli-hánánì sì kú, Hádádì sì di ọba nípò Rẹ̀. Orúkọ ìlú Rẹ̀ sì ni Páì; àti orúkọ ìyàwó sì ni Méhélábélì ọmọbìnrin Métírédì, ọmọbìnrin Mésíhábù.

51. Hádádì sì kú pẹ̀lú.Àwọn olórí Édómù ni:Tímínà, Álífà, Jététì

52. Óhólíbámà, Élà, Pínónì.

1 Kíróníkà 1