1 Kíróníkà 1:23-39 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

23. Ófírì, Háfílà, àti Jóbábù. Gbogbo àwọn wọ̀nyí sì jẹ́ àwọn ọmọ Jókítanì.

24. Ṣémù, Árífákásádì, Sẹ́bà,

25. Ébérì, Pélégì. Réù,

26. Ṣérúgì, Náhórì, Térà:

27. Àti Ábúrámù (tí ń ṣe Ábúráhámù).

28. Àwọn ọmọ Ábúráhámù:Ísáákì àti Íṣímáẹ́lì.

29. Èyí ni àwọn ọmọ náà:Nébáíótì àkọ́bí Íṣímáẹ́lì: Kédárì, Ádíbélì, Míbísámù,

30. Míṣímà, Dúmà, Másà, Hádádì, Témà,

31. Jétúrì, Náfísì, àti Kédámù. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Íṣímáẹ́lì

32. Àwọn ọmọ Kétúrà, obìnrin Ábúráhámù:Símíránì, Jókíṣánì Médánì, Mídíánì Iṣíbákì àti Ṣúà.Àwọn ọmọ Jókísánì:Ṣébà àti Dédánì.

33. Ọmọ Mídíánì:Éfà. Hénókì, Éférì, Ábídà àti Élídà.Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ìran Kétúrà.

34. Ábúráhámù sì jẹ́ baba Ísáákì:Àwọn ọmọ Ísáákì:Ísọ̀ àti Ísírẹ́lì.

35. Àwọn ọmọ Ísọ̀:Élífásì, Réuélì, Jéúsì, Jálámù, àti Kórà.

36. Àwọn ọmọ Élífásì:Témánì, Ómárì, Ṣéfì, Gátamù àti Kénásì;làti Tímánà: Ámálékì.

37. Àwọn ọmọ Réúélì:Náhátì, Ṣérà, Ṣámà àti Mísà.

38. Àwọn ọmọ Ṣéírì:Lótanì, Ṣóbálì, Ṣíbéónì, Ánà, Díṣónì, Ésárì àti Dísánì.

39. Àwọn ọmọ Lótanì:Hórì àti Hómámù. Tímínà sì jẹ́ arábìnrin Lótanì.

1 Kíróníkà 1