O. Daf 48:5-8 Yorùbá Bibeli (YCE)

5. Nwọn ri i, bẹ̃li ẹnu yà wọn; a yọ wọn lẹnu, nwọn yara lọ.

6. Ẹ̀ru bà wọn nibẹ, ati irora bi obinrin ti nrọbi.

7. Iwọ fi ẹfufu ila-õrun fọ́ ọkọ Tarṣiṣi.

8. Bi awa ti gbọ́, bẹ̃li awa ri ni ilu Oluwa awọn ọmọ-ogun, ni ilu Ọlọrun wa: Ọlọrun yio gbé e kalẹ lailai.

O. Daf 48