O. Daf 119:17-21 Yorùbá Bibeli (YCE)

17. Fi ọ̀pọlọpọ ba iranṣẹ rẹ ṣe, ki emi ki o le wà lãye, ki emi ki o le ma pa ọ̀rọ rẹ mọ́.

18. Là mi li oju, ki emi ki o le ma wò ohun iyanu wọnni lati inu ofin rẹ.

19. Alejo li emi li aiye: máṣe pa àṣẹ rẹ mọ́ fun mi.

20. Aiya mi bù nitori ifojusọna si idajọ rẹ nigbagbogbo.

21. Iwọ ti ba awọn agberaga wi, ti a ti fi gégun, ti o ti ṣina kuro nipa aṣẹ rẹ.

O. Daf 119