Samuẹli Keji 5:14-17 BIBELI MIMỌ (BM)

14. Orúkọ àwọn tí wọ́n bí fún un ní Jerusalẹmu nìwọ̀nyí: Ṣamua ati Ṣobabu, Natani, ati Solomoni;

15. Ibihari ati Eliṣua, Nefegi ati Jafia;

16. Eliṣama, Eliada, ati Elifeleti.

17. Nígbà tí àwọn ará Filistia gbọ́ pé wọ́n ti fi Dafidi jọba Israẹli, gbogbo àwọn ọmọ ogun wọn jáde lọ láti mú un, ṣugbọn Dafidi gbọ́ pé wọ́n ń bọ̀ wá mú òun, ó bá lọ sí ibi ààbò.

Samuẹli Keji 5